الناس
An-Nas
Mankind
1 - An-Nas (Mankind) - 001
قُلۡ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلنَّاسِ
Sọ pé: “Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,
2 - An-Nas (Mankind) - 002
مَلِكِ ٱلنَّاسِ
Ọba àwọn ènìyàn,
3 - An-Nas (Mankind) - 003
إِلَٰهِ ٱلنَّاسِ
Ọlọ́hun àwọn ènìyàn,[1]
1. Ìtúmọ̀ “Ọlọ́hun àwọn ènìyàn” ni pé, Ẹni tí àwọn ènìyàn gbọ́dọ̀ máa jọ́sìn fún ní ọ̀nà òdodo, tí wọn kò sì gbọ́dọ̀ jọ́sìn fún ẹlòmíìràn lẹ́yìn Rẹ̀.
4 - An-Nas (Mankind) - 004
مِن شَرِّ ٱلۡوَسۡوَاسِ ٱلۡخَنَّاسِ
níbi aburú (aṣ-Ṣaetọ̄n) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni tó bá ń dárúkọ Allāhu[1]).
1. Ọ̀kan pàtàkì nínú àǹfààní àti oore tí ó wà nínú ath-thikār ṣíṣe ni pé, aṣ-Ṣaetọ̄n àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ yóò máa sá sẹ́yìn fún ẹni tí ó bá ń ṣe ath-thikār ní gbogbo ìgbà.
5 - An-Nas (Mankind) - 005
ٱلَّذِي يُوَسۡوِسُ فِي صُدُورِ ٱلنَّاسِ
(aṣ-Ṣaetọ̄n ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.
6 - An-Nas (Mankind) - 006