HadeethEnc · 1.14.0
Gigiṣẹ ẹru kan konii bu fún erukuru ni ojú ọna Ọlọhun ki iná wa jo
Available translations
Choose an available translation of this Hadeeth
01
Hadeeth text
Láti ọdọ bàbá Absin Abdur-rahman ọmọ Jabr - kí Ọlọhun yọnu si - dájúdájú òjíṣẹ Ọlọhun - kí ikẹ Ọlọhun ati ọla Rẹ máa ba a - sọ pé: "Gigiṣẹ ẹru kan konii bu fún erukuru ni ojú ọna Ọlọhun ki iná wa jo".
02
Explanation
Òjíṣẹ Ọlọhun (kí ikẹ Ọlọhun ati ọla Rẹ máa ba a) fún wa ní ìró idunnu pé ẹni tí eruku bá bo ẹsẹ rẹ mejeeji nígbàtí o njagun sí oju-ọna Ọlọhun pe iná kò ní jó ẹni na.
03
Benefits
ìfunni ní ìró idunnu fún olujagun sí ojú ọna Ọlọhun pe yóò rí ìgbàlà ati àkóyọ níbi Iná.
Anọbi darukọ gigisẹ mejeeji bó ti ẹ jẹ pé erukuru náà yóò kárí gbogbo ara lapapọ; nitoripé ọpọlọpọ awọn olujagun nigbà náà ni wọn nfi ẹsẹ rìn, ti gigiṣẹ wọn yóò sì kó eruku ni gbogbo iṣesí.
Ibn Hajar ṣọ pe: ti o bá ṣe pé kí eruku kan gigisẹ lasan ni yóò ṣe iná leewọ fún ni, bá wo wa ni ti ẹni ti o bá ṣe akitiyan ti o tun lo igbiyanju rẹ, ti o si lo gbogbo oun tó ní nikapa.
Anọbi darukọ gigisẹ mejeeji bó ti ẹ jẹ pé erukuru náà yóò kárí gbogbo ara lapapọ; nitoripé ọpọlọpọ awọn olujagun nigbà náà ni wọn nfi ẹsẹ rìn, ti gigiṣẹ wọn yóò sì kó eruku ni gbogbo iṣesí.
Ibn Hajar ṣọ pe: ti o bá ṣe pé kí eruku kan gigisẹ lasan ni yóò ṣe iná leewọ fún ni, bá wo wa ni ti ẹni ti o bá ṣe akitiyan ti o tun lo igbiyanju rẹ, ti o si lo gbogbo oun tó ní nikapa.
Attribution
[Bukhaariy gba a wa]
Categories
Share
Share hadeeth
Sharing options · 0 Total shares

