Èmi ni Olùrọrọ̀ julọ tayọ níní orogún. Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe iṣẹ́ kan, ti o mu orogun ninu rẹ̀ pẹlu Èmi Ọlọhun, Emi yóò fi òun àti orogun rẹ̀ sílẹ̀
Choose an available translation of this Hadeeth
Hadeeth text
Lati ọdọ Abu Hurairah, ki Ọlọhun yọnu si i, o sọ pe: Ojiṣẹ Ọlọhun, ki ikẹ ati ọla Ọlọhun maa ba a, sọ pe: “Ọlọhun, Oníbùkún ti O ga jùlọ, sọ pe: Èmi ni Olùrọrọ̀ julọ tayọ níní orogún. Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe iṣẹ́ kan, ti o mu orogun ninu rẹ̀ pẹlu Èmi Ọlọhun, Emi yóò fi òun àti orogun rẹ̀ sílẹ̀.
Explanation
Benefits
Níní ìmọ̀lára ọrọ̀ Ọlọhun ati titobi Rẹ̀, ó wà ninu awọn nkan tó máa n ṣe iranlọwọ lati jẹ ki a ṣe iṣẹ ní mimọ fun Ọlọhun.
Attribution
Categories
Share hadeeth
Sharing options · 0 Total shares

